Laipe yii ni Gomina Ipinle Rivers to tun je oludari ipolongo idibo fun oludije fun ipo Aare labe egbe oselu APC, Ogbe Rotimi Amaechi fesun kan awon pasito kan wi pe won gba owo bi bilionu mefa owo naira lowo Goodluck Jonathan lati tako Muhammodu Buhari.
O dabi eni wi pe otito ni oro naa fe e je. Nitori oludari ijo Irapada (Redeemed Christian Church of God), Pastor Enoch Adeboye ti kede wi pe taa ba ri pasito kankan to ba gba iru owo bee ko tete daapada bi owo baba Ijebu ko to di wi pe ina Olorun yoo da le lori.
"I read in the newspaper this morning that one of the serving governors in Nigeria said that some pastors in Nigeria collected N6bn from politicians for the purpose of influencing their members to vote a certain candidate in the coming elections.
"May I humbly request that if there be any pastor or pastors who collected such money, they should please return such as quickly as possible before the fire of the Almighty consumes you." Pasito E.A. Adeboye
Home / Uncategories / "Ina Olorun Yoo Jo Pasito To Ba Gba Bilionu Mefa Lowo Oloselu Lati Si Awon Eniyan Lona" - Adeboye
Subscribe to:
Post Comments
(
Atom
)
0 comments:
Post a Comment