Báyìí ni Ààrẹ Buhari ṣe yẹ̀yẹ́ àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà ni ilu London Olayemi Oniroyin 4/20/2018 08:48:00 am Add Comment Edit "Nnkan ọ̀fẹ́ tí baye àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà jẹ. Wọn kò fẹ ohunkóhun ṣe, gbogbo ìgbà, sáà-ba-n-mu lorin tí wọn kọ. Bí sádákà, bí ìfà ni wọn... Read More
Lẹ́yìn Ọlọ́run ìyàwó mi lo kan - Yemi Solade Olayemi Oniroyin 4/19/2018 01:36:00 am Add Comment Edit Yemi Solade lọ ṣe àfihàn ìyàwó rè pelu akole tó sọ wí pé, lẹ́yìn Ọlọ́run ìyàwó òun ni ènìyàn tó kàn ninu igbe ayé òun. Read More
Àwọn ọlọ́pàá tí gbé Senator Ovie Omo Agege to kò àwọn ọmọ ìta wọlé igbimo asofin Olayemi Oniroyin 4/19/2018 01:35:00 am Add Comment Edit Laarọ yìí ni àwọn ọmọ ìta yawọ ilé igbimo asofin àgbà Abuja tí wọn sì jí ọ̀pá àṣẹ sálọ. Ní báyìí àwọn ọlọ́pàá tí gbé Senator Ovie Omo Agege ... Read More