Hubert Ogunde: Ohun tí àwọn onsọ̀tàn sọ nípa ìbẹ̀rẹ̀ tíátà Nigeria Olayemi Oniroyin 9/26/2019 10:58:00 am Add Comment Edit Hubert Ogunde Ko ̀ si ́ bi ́ a s ̣ e fe ̣ ki ́ Ì ba ̀ da ̀ n la ́ i ̀ me ̣́ nu ba àru ̀ n Ìba ̀ da ̀ n; sebi ́ wo ̣́ n... Read More
Wizkid bale ọba jẹ nílùú London! Olayemi Oniroyin 5/28/2018 10:06:00 am Add Comment Edit Omilẹgbẹ èrò bí ọjọ́ àjíǹde ni wọn ya wo 02 Arena láti wá wòran Ayodeji ọmọ ológo dídán. Igba àkọ́kọ́ ni yìí nílùú London ti onkorin ilé adú... Read More
Ọkùnrin ní má fi oyún inú mi bí - @LindaIkeji Olayemi Oniroyin 5/21/2018 10:55:00 am Add Comment Edit "Mi ò lè pa ayọ̀ yìí mora mọ. Ìdùnnú mi lo jẹ láti kéde rẹ fún yín wí pé, àkọ́bí ọmọ mi kò ní pẹ́ de ba mi lálejò ni nǹkan bí oṣù kan s... Read More
"Ojú tí Nìyí, Toyin Abraham ti pàdé ọkọ tuntun oloriire" - Àwọn tí Toyin fò fáyọ̀ Olayemi Oniroyin 5/21/2018 10:42:00 am Add Comment Edit "Ojú ti Nìyí aronipin! " Awọn olólùfẹ́ Toyin Abraham ti gbogbo ènìyàn mọ sì Toyin Aimakhu tẹ́lẹ̀ tí ń bá yọ báyìí pẹ̀lú bi òṣerébì... Read More
Foto ètò ìsìnkú Aisha Abimbola nílùú Canada Olayemi Oniroyin 5/18/2018 10:21:00 am Add Comment Edit Read More
Ìrántí ọdún kan Moji Olaiya wáyé lẹ́yìn ìsìnkú Aisha Abimbola Olayemi Oniroyin 5/17/2018 11:38:00 pm Add Comment Edit Moji Olaiya tí pé ọdún kan báyìí. Aisha Abimbola lọ ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò tiẹ̀ sóde ọ̀run ni. Ta wá ni ènìyàn tí kò ní kú? Àdúrà wa kan ni w... Read More
Ọ̀rọ̀ tí Aisha Abimbola sọ kẹyin lórí whatsapp kó to kú ní yìí Olayemi Oniroyin 5/16/2018 08:40:00 pm Add Comment Edit Ali Baba, ogbontarigi alawada ilẹ̀ Nàìjíríà tí ṣe àfihàn itakurọsọ to wáyé kẹyin láàárín òun àti olóògbé Aisha Abimbola. Nínú itakurọsọ orí... Read More
Ìgbéyàwó òṣerébìnrin onitia míì tí tú ká? Ohun tí Ìrètí Osayemi sọ nípa ìdílẹ̀ rẹ ni yìí Olayemi Oniroyin 5/16/2018 07:31:00 pm Add Comment Edit Orisirisi ahesọ ọ̀rọ̀ lọ tí kún ìgboro báyìí wí pé òṣerébìnrin Ìrètí Osayemi náà tí pàdánù ìgbéyàwó rẹ pẹlu Bakare Adeoye. Ṣùgbọ́n sá, àwọn... Read More
"Odunlade ò rí pátá mi rí" - Eniola Ajao Olayemi Oniroyin 5/16/2018 02:37:00 pm Add Comment Edit Eniola Ajaola tí sọ ọ kedere wí pé kò sí ajosepo lọkọlaya láàárín òun àti Odunlade Adekola. Nínú ifọrọwero pẹ̀lú òṣerébìnrin yìí ló ti se à... Read More
Aisha Abimbola (Ọmọge Campus) tí kọjá sọ́run nílùú Canada Olayemi Oniroyin 5/16/2018 01:54:00 pm Add Comment Edit Òṣerébìnrin ilẹ̀ Nàìjíríà, Aishat Abimbola tí gbogbo ènìyàn mo sì ọmọge Campus tí papoda lọ́jọ́ mẹẹdogun oṣù karùn-ún ọdún 2018. Òṣeré náà ... Read More
City People Magazine ṣetán láti dá Adegbodu Twins lọ́lá Olayemi Oniroyin 5/11/2018 02:54:00 pm Add Comment Edit Awon Aláṣẹ City People Magazine tí ṣetan láti ṣe ayẹyẹ idalọla fún àwọn ìbejì Adegbodu fún ipa ribiribi tí wón tí kò ti a ba n sọ nípa ojúló... Read More
Aṣọ Mercy Aigbe to dá wàhálà silẹ ni yìí Olayemi Oniroyin 5/10/2018 11:08:00 pm Add Comment Edit Àríyá... níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Kemi Afolabi. Àwọn ènìyàn sọ wí pé aṣọ ti Mercy Aigbe wọ kò dára tó nígbà ti àwọn kan rí gẹ́gẹ́ bí oge lásán el... Read More
Odunlade Adekola yege: Irawo osere náà kàwé gboyè Olayemi Oniroyin 5/10/2018 11:01:00 pm Add Comment Edit Kò sí ìgbà táa dásọ tá rilẹ fiwọ́. Odunlade Adekola tí padà kàwé gboyè. Congratulations 🎊 Read More
Àṣírí isẹ tíátà Olayemi Oniroyin 4/25/2018 12:36:00 pm Add Comment Edit Asaraloge nínú ìṣe tíátà tí rekoja ká kún àtíkè funfun sì osere lójú, àwọn asaraloge to bá sha pra pra wọn a tún má sẹ da ẹ̀yà ara ènìyàn. O... Read More
Ohun tí ẹ kò mọ nípa Ayodeji Ibrahim Balogun (Wizkid) Olayemi Oniroyin 4/23/2018 01:11:00 pm Add Comment Edit Ohun tí ẹ kò mọ nípa Ayodeji Ibrahim Balogun (Wizkid) láti ọwọ́ Olayemi Olatilewa (Olayemi Oniroyin) Ọdún1990 ni wọn bí si ìdílé musulumi ... Read More
Lẹ́yìn Ọlọ́run ìyàwó mi lo kan - Yemi Solade Olayemi Oniroyin 4/19/2018 01:36:00 am Add Comment Edit Yemi Solade lọ ṣe àfihàn ìyàwó rè pelu akole tó sọ wí pé, lẹ́yìn Ọlọ́run ìyàwó òun ni ènìyàn tó kàn ninu igbe ayé òun. Read More
Ọkùnrin to kọ mi silẹ lọ fẹ ọmọ komisanna tí di ọlọkada bayii- Liz Anjorin Olayemi Oniroyin 4/01/2018 01:32:00 pm Add Comment Edit Ọmọkùnrin kan lọ ń kabamọ lórí ayélujára wí pé òun ni àǹfààní láti fẹ́ ọmọ Dangote nígbà ti àwọn se agunbaniro ṣùgbọ́n sẹnsi òun kò ṣíṣe dáa... Read More
Lọ́jọ́ tí wọn fi Femi Branch jẹ Jagun Asa Olayemi Oniroyin 3/31/2018 07:30:00 am Add Comment Edit Won ni bí a kò ba rí ẹyẹ igun a gbọ́dọ̀ ṣebọ, bí a kò rí ẹyẹ akala a gbọdọ sorò, bí a kò bá ti rí ewé akòko kò sí bá a ti fẹ́ joyè nílẹ̀ yìí... Read More
Muyiwa Ademola tí padà sí kíláàsì gẹ́gẹ́ bí olùkọ́ Olayemi Oniroyin 3/16/2018 03:37:00 am Add Comment Edit Kosi bí ènìyàn tí wù kó lọ́gbọ́n tàbí ní imọ, tí ẹnì náà kò ba ni ifarabalẹ, yóò nira fún irú ẹni bẹẹ láti sọ alaimọkan di onímò kíkún. Yàt... Read More
"Kosi ohun tó kàn mí pelu ayé Nìyí" - Toyin Abraham fàbínú yọ Olayemi Oniroyin 3/11/2018 02:47:00 pm Add Comment Edit Nígbà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ń ro wí pé wàhálà láàárín Toyin Abraham àti Adeniyi Johnson tí rodo lọ mú mi, rúgúdù míì tú dabi wí pé ó fẹ́ súyọ pelu è... Read More