Wàhálà NURTW: Alh Akanni Olohunwa tí wọ gau!. pt3 Olayemi Oniroyin 2/18/2018 05:09:00 pm Add Comment Edit Adé Lawyer, ẹni tó sọ wí pé Alaaji Akanni Olohunwa lo rán òun láti ṣekú pa Kunle Poly kò ti dake àlàyé rẹ. "Kunle Poly là fẹ́ pa, Pine... Read More
Wàhálà NURTW: Alh Akanni Olohunwa tí wọ gau! pt2 Olayemi Oniroyin 2/18/2018 04:20:00 pm Add Comment Edit Nígbà tí Ade Lawyer ri wí pé òpin tí de, gbogbo ohun tó pamọ pátá lo ṣàlàyé fun àwọn oniroyin. Alaye ògbólógbòó agbanipa náà ní yìí: "... Read More
Wàhálà NURTW: Alh Akanni Olohunwa tí wọ gau! Olayemi Oniroyin 2/18/2018 04:00:00 pm Add Comment Edit Akíkanjú olopaa ọlọtẹlẹmuyẹ to mú ògbólógbòó ọ̀daràn tí ń jẹ Evans nijosi, Abba Kyari tí mú ọkùnrin kan tí ń jẹ Adeola Williams, ẹni tí inag... Read More
Ẹ̀jẹ̀ san ni Zamfara: 41 ènìyàn tí wọlẹ̀ sún lójú bajinatu àwọn odaju ẹ̀dá Olayemi Oniroyin 2/18/2018 06:38:00 am Add Comment Edit Ni Ipinle Zamfara, n se ni wọn tẹ òkú àwọn ènìyàn sílè bí ìgbà tí wọn ba le ìṣù sílè loja oritamerin Ibadan. Bi ènìyàn bá dé ijoba ibile Bir... Read More
Lẹta mi sí Yakubu Fanami tí Boko Haram ṣekú pa Olayemi Oniroyin 2/05/2018 06:03:00 pm Add Comment Edit Yakubu, mi ò mọ bóyá wà ni anfaani lati ká leta mi yii. Ṣùgbọ́n mo fi dá ọ lójú wí pé, má gun orí òkè méje, máa sì kó orúkọ rẹ sì ọna méje ... Read More